1 Ègbé ni fún ilẹ̀ tí ó kún fún ariwo ìyẹ́ eṣú,
2 tí ó rán àwọn ikọ̀ lórí Òkun
3 Gbogbo ẹ̀yin ènìyàn ayé,
4 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi:
5 Nítorí, kí ìkórè tó bẹ̀rẹ̀,
6 A ó fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn ẹyẹ òkè ńlá
7 Ní àkókò náà ni a ó mú ẹ̀bùn wá fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun