1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Damasku:
2 Àwọn ìlú Aroeri ni a ó kọ̀sílẹ̀
3 Ìlú olódi ni yóò pòórá kúrò ní Efraimu,
4 “Ní ọjọ́ náà ni ògo Jakọbu yóò sá;
5 Yóò sì dàbí ìgbà tí olùkórè kó àwọn
6 Síbẹ̀síbẹ̀ irúgbìn díẹ̀ yóò ṣẹ́kù,
7 Ní ọjọ́ náà, àwọn ènìyàn yóò gbójú sókè sí Ẹlẹ́dàá wọn,
8 Wọn kò ní wo àwọn pẹpẹ mọ́,
9 Ní ọjọ́ náà àwọn ìlú alágbára rẹ̀, yóò dàbí ẹ̀ka ìkọ̀sílẹ̀, àti ẹ̀ka téńté òkè tí wọ́n fi sílẹ̀ nítorí àwọn ọmọ Israẹli. Gbogbo wọn yóò sì di ahoro.
10 Nítorí ìwọ ti gbàgbé Ọlọ́run ìgbàlà rẹ;
11 Nítorí náà, bí ẹ tilẹ̀ mú àṣàyàn igi tí ẹ sì gbin àjàrà tí ó ti òkèrè wá,
12 Kíyèsi i, ìrunú àwọn orílẹ̀-èdè—
13 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ènìyàn ń bú
14 Ní aginjù, ìpayà òjijì!