Isaías 14

YOR

1 Olúwa yóò fi àánú hàn fún Jakọbu,

2 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbà wọ́n

3 Ní ọjọ́ tí Olúwa yóò fi ìtura fún un yín kúrò nínú ìpọ́njú àti ìyà àti ìdè ìkà,

4 ẹ ó sì fi ọ̀rọ̀ àbùkù yìí kan ọba Babeli pé,

5 Olúwa ti dá ọ̀pá ìkà náà,

6 èyí tí ó ti lu àwọn ènìyàn bolẹ̀

7 Gbogbo ilẹ̀ ni ó wà ní ìsinmi àti àlàáfíà,

8 Pẹ̀lúpẹ̀lú àwọn igi junifa àti àwọn

9 Ibojì tí ó wà ní ìsàlẹ̀ ni a ru sókè

10 Gbogbo wọn yóò dáhùn,

11 Gbogbo rẹ̀ ni ó di ìrẹ̀sílẹ̀ lọ sí ibojì,

12 Báwo ni ìwọ ṣe ṣubú lulẹ̀ láti ọ̀run wá,

13 Ìwọ sọ nínú ọkàn rẹ pé,

14 Èmi yóò gòkè lọ rékọjá àwọn àwọsánmọ̀;

15 Ṣùgbọ́n a ti rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ wọ inú ibojì lọ

16 Àwọn tí ó rí ọ yóò tẹjúmọ́ ọ,

17 Ẹni tí ó sọ ayé di aginjù,

18 Gbogbo àwọn ọba orílẹ̀-èdè ni a tẹ́ sílẹ̀

19 Ṣùgbọ́n a jù ọ́ síta kúrò nínú ibojì

20 a kò ní sin ọ́ pẹ̀lú wọn,

21 Tọ́jú ibìkan tí a ó ti pa àwọn ọmọkùnrin rẹ

22 “Èmi yóò dìde sókè sí wọn,”

23 Èmi yóò yí i padà sí ibùgbé àwọn òwìwí

24 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti búra,

25 Èmi yóò run Asiria ní ilẹ̀ mi,

26 Èyí ni ètò tí a pinnu rẹ̀ fún gbogbo ayé,

27 Nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti pète,

28 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ yí wá ní ọdún tí ọba Ahasi kú.

29 Má ṣe yọ̀, gbogbo ẹ̀yin Filistia,

30 Ẹni tí ó kúṣẹ̀ẹ́ jù yóò ní pápá oko,

31 Hu, ìwọ ẹnu-ọ̀nà! Kígbe, ìwọ ìlú!

32 Kí ni ìdáhùn tí a ó fún

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado