1 Èyí ni ìbùkún tí Mose ènìyàn Ọlọ́run bùkún fún àwọn ọmọ Israẹli kí ó tó kú.
2 Ó sì wí pé,
3 Nítòótọ́, ó fẹ́ràn àwọn ènìyàn an rẹ̀,
4 òfin tí Mose fi fún wa,
5 Òun ni ọba lórí Jeṣuruni
6 “Jẹ́ kí Reubeni yè kí ó má ṣe kú,
7 Èyí ni ohun tí ó sọ nípa Juda:
8 Ní ti Lefi ó wí pé,
9 Ó wí fún baba àti ìyá rẹ pé,
10 Ó kọ́ Jakọbu ní ìdájọ́ rẹ̀
11 Bùsi ohun ìní rẹ̀, Olúwa,
12 Ní ti Benjamini ó wí pé,
13 Ní ti Josẹfu ó wí pé,
14 àti fún èso iyebíye tí ọ̀run mú wá
15 pẹ̀lú ohun pàtàkì òkè ńlá ìgbàanì
16 Pẹ̀lú ohun iyebíye ayé àti ẹ̀kún un rẹ̀
17 Ní ọláńlá ó dàbí àkọ́bí akọ màlúù;
18 Ní ti Sebuluni ó wí pé,
19 Wọn yóò pe àwọn ènìyàn sórí òkè
20 Ní ti Gadi ó wí pé,
21 Ó sì yan ilẹ̀ tí ó dára jù fún ara rẹ̀;
22 Ní ti Dani ó wí pé,
23 Ní ti Naftali ó wí pé,
24 Ní ti Aṣeri ó wí pé,
25 Bàtà rẹ̀ yóò jẹ́ irin àti idẹ,
26 “Kò sí ẹlòmíràn bí Ọlọ́run Jeṣuruni,
27 Ọlọ́run ayérayé ni ibi ìsádi rẹ,
28 Israẹli nìkan yóò jókòó ní àlàáfíà,
29 Ìbùkún ni fún ọ, Israẹli,