1 Ní orí ibùsùn mi ní òru
2 Èmi yóò dìde nísinsin yìí, èmi yóò sì rìn lọ káàkiri ìlú,
3 Àwọn ọdẹ tí ń ṣọ́ ìlú rí mi
4 Gẹ́rẹ́ tí mo fi wọ́n sílẹ̀
5 Ẹ̀yin ọmọbìnrin Jerusalẹmu,
6 Ta ni ẹni tí ń ti ijù jáde wá
7 Wò ó! Àkéte rẹ̀ tí í ṣe ti Solomoni,
8 gbogbo wọn ni ó mú idà lọ́wọ́,
9 Solomoni ọba ṣe àkéte fún ara rẹ̀;
10 Ó fi fàdákà ṣe òpó rẹ̀,
11 Ẹ jáde wá, ẹ̀yin ọmọbìnrin Sioni,