1 Crônicas 2

YOR

1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Israẹli. Reubeni, Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Sebuluni,

2 Dani, Josẹfu, Benjamini; Naftali, Gadi: àti Aṣeri.

3 Àwọn ọmọ Juda:

4 Tamari, aya ọmọbìnrin Juda, ó sì bí Peresi àti Sera sì ní ọmọ márùn-ún ní àpapọ̀.

5 Àwọn ọmọ Peresi:

6 Àwọn ọmọ Sera:

7 Àwọn ọmọ Karmi:

8 Àwọn ọmọ Etani:

9 Àwọn ọmọ tí a bí fún Hesroni ni:

10 Ramu sì ni baba Amminadabu,

11 Nahiṣoni sì ni baba Salmoni,

12 Boasi baba Obedi

13 Jese sì ni baba

14 ẹlẹ́ẹ̀kẹrin Netaneli,

15 ẹlẹ́ẹ̀kẹfà Osemu

16 Àwọn arábìnrin wọn ni Seruiah àti Abigaili.

17 Abigaili ni ìyá Amasa, ẹni tí baba rẹ̀ sì jẹ́ Jeteri ará Iṣmaeli.

18 Kalebu ọmọ Hesroni ní ọmọ láti ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ Asuba (láti ọ̀dọ̀ Jerioti). Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ rẹ̀:

19 Nígbà tí Asuba sì kú, Kalebu sì fẹ́ Efrata ní aya, ẹni tí ó bí Huri fún un.

20 Huri ni baba Uri, Uri sì jẹ́ baba Besaleli.

21 Nígbà tí ó yá, Hesroni sì dùbúlẹ̀ pẹ̀lú ọmọbìnrin Makiri baba Gileadi (ó sì ti fẹ́ ní aya láti ìgbà tí ó ti wà ní ẹni ọgọ́ta ọdún) ó sì bí Segubu.

22 Segubu sì jẹ́ baba Jairi, ẹni tí ó jẹ́ olùdarí ìlú mẹ́tàlélógún ní ilẹ̀ Gileadi.

23 (Ṣùgbọ́n Geṣuri àti Aramu sì fi agbára gba Hafoti-Jairi, àti Kenati pẹ̀lú gbogbo agbègbè rẹ̀ tí wọn tẹ̀dó sí jẹ́ ọgọ́ta ìlú.)

24 Lẹ́yìn tí Hesroni sì kú ni Kalebu Efrata, Abijah ìyàwó rẹ̀ ti Hesroni sì bí Aṣihuri baba Tekoa fún un.

25 Ọmọ Jerahmeeli àkọ́bí Hesroni:

26 Jerahmeeli ní ìyàwó mìíràn, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Atara; ó sì jẹ́ ìyá fún Onamu.

27 Àwọn ọmọ Ramu àkọ́bí Jerahmeeli:

28 Àwọn ọmọ Onamu:

29 Orúkọ ìyàwó Abiṣuri ni Abihaili ẹni tí ó bí Ahbani àti Molidi.

30 Àwọn ọmọ Nadabu

31 Àwọn ọmọ Appaimu:

32 Àwọn ọmọ Jada, arákùnrin Ṣammai:

33 Àwọn ọmọ Jonatani:

34 Ṣeṣani kò sì ní ọmọkùnrin àwọn ọmọbìnrin nìkan ni ó ní.

35 Ṣeṣani sì fi ọmọ obìnrin rẹ̀ ní aya fún ìránṣẹ́ rẹ̀ Jariha, ó sì bí ọmọ fún tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ Attai.

36 Attai sì jẹ́ baba fún Natani,

37 Sabadi ni baba Eflali,

38 Obedi sì ni baba Jehu,

39 Asariah sì ni baba Helesi,

40 Eleasa ni baba Sismai,

41 Ṣallumu sì ni baba Jekamiah,

42 Àwọn ọmọ Kalebu arákùnrin Jerahmeeli:

43 Àwọn ọmọ Hebroni:

44 Ṣema ni baba Rahamu,

45 Àwọn ọmọ Ṣammai ni Maoni,

46 Efani obìnrin Kalebu sì ni ìyá

47 Àwọn ọmọ Jahdai:

48 Maaka obìnrin Kalebu sì ni ìyá

49 Ó sì bí Ṣaafu baba Madmana,

50 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Kalebu.

51 Salma baba Bẹtilẹhẹmu àti Harefu baba Beti-Gaderi.

52 Àwọn ọmọ Ṣobali baba Kiriati-Jearimu ni:

53 Àti ìdílé Kiriati-Jearimu: àti àwọn ara Itri, àti àwọn ará Puti, àti àwọn ará Ṣumati àti àwọn ará Miṣraiti: láti ọ̀dọ̀ wọn ni àwọn ọmọ ará Sorati àti àwọn ará Eṣtaoli ti wá.

54 Àwọn ọmọ Salma:

55 àti àwọn ìdílé àwọn akọ̀wé, ẹni tí ń gbé ní Jabesi: àti àwọn ọmọ Tirati àti àwọn ará Ṣimeati àti àwọn ará Sukati. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ará Keni, ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Hamati, baba ilé Rekabu.

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado