1 Gbọ́, Olúwa, kí o sì dá mi lóhùn,
2 Dáàbò bò ayé mi, nítorí a ti yà mí sọ́tọ̀ fún ọ:
3 Ṣàánú fún mi, Olúwa,
4 Mú ayọ̀ wà fún ìránṣẹ́ rẹ,
5 Ìwọ ń dáríjì, ìwọ sì dára, Olúwa,
6 Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa;
7 Ní ọjọ́ ìpọ́njú mi èmi yóò pè ọ́,
8 Nínú àwọn òrìṣà kò sí ẹni tí ó dàbí i rẹ, Olúwa:
9 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ dá
10 Nítorí pé ìwọ tóbi, ìwọ sì ń ṣe ohun ìyanu;
11 Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, Olúwa,
12 Èmi ó yìn ọ́, Olúwa Ọlọ́run mi, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi;
13 Nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ si mi;
14 Àwọn onígbèéraga ń dojúkọ mí, Ọlọ́run;
15 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, jẹ́ aláàánú àti Ọlọ́run olójúrere,
16 Yípadà sí mi kí o sì ṣàánú fún mi;
17 Fi àmì hàn mí fún rere,