Salmos 86

YOR

1 Gbọ́, Olúwa, kí o sì dá mi lóhùn,

2 Dáàbò bò ayé mi, nítorí a ti yà mí sọ́tọ̀ fún ọ:

3 Ṣàánú fún mi, Olúwa,

4 Mú ayọ̀ wà fún ìránṣẹ́ rẹ,

5 Ìwọ ń dáríjì, ìwọ sì dára, Olúwa,

6 Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa;

7 Ní ọjọ́ ìpọ́njú mi èmi yóò pè ọ́,

8 Nínú àwọn òrìṣà kò sí ẹni tí ó dàbí i rẹ, Olúwa:

9 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ dá

10 Nítorí pé ìwọ tóbi, ìwọ sì ń ṣe ohun ìyanu;

11 Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, Olúwa,

12 Èmi ó yìn ọ́, Olúwa Ọlọ́run mi, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi;

13 Nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ si mi;

14 Àwọn onígbèéraga ń dojúkọ mí, Ọlọ́run;

15 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, jẹ́ aláàánú àti Ọlọ́run olójúrere,

16 Yípadà sí mi kí o sì ṣàánú fún mi;

17 Fi àmì hàn mí fún rere,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado