1 Aṣiwèrè wí nínú ọkàn rẹ̀ pé,
2 Olúwa sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run wá
3 Gbogbo wọn sì ti yípadà, gbogbo wọn sì ti díbàjẹ́;
4 Ǹjẹ́ olùṣe búburú kò ha ní ìmọ̀?
5 Wọ́n wà níbẹ̀, tí a bò mọ́lẹ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù,
6 Ẹ̀yin olùṣe búburú da èrò àwọn tálákà rú,
7 Ìgbàlà àwọn Israẹli yóò ti Sioni wá!