1 “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,”
2 ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa,
3 nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè
4 nígbà náà ni omi
5 nígbà náà ni agbéraga
6 Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n
7 Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ;
8 Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa,