1 Ràn wá lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kò sí mọ́;
2 Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀;
3 Kí Olúwa kí ó gé ètè èké wọn
4 tí ó wí pé,
5 “Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní,
6 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù,
7 Olúwa, ìwọ yóò pa wá mọ́
8 Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri