Salmos 12

YOR

1 Ràn wá lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kò sí mọ́;

2 Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀;

3 Kí Olúwa kí ó gé ètè èké wọn

4 tí ó wí pé,

5 “Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní,

6 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù,

7 Olúwa, ìwọ yóò pa wá mọ́

8 Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado