1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
2 Irú-ọmọ rẹ̀ yóò jẹ́ alágbára ní ayé:
3 Ọlá àti ọrọ̀ yóò wà nínú ilé rẹ̀;
4 Fún olóòótọ́ ni ìmọ́lẹ̀ yóò tàn fún ní òkùnkùn:
5 Ènìyàn rere fi ojúrere hàn,
6 Dájúdájú a kì yóò le yí ní ipò padà láéláé:
7 Òun kì yóò béèrè ìyìn búburú:
8 Ó ti mú ọkàn rẹ̀ gbilẹ̀, ẹ̀rù kí yóò bà á,
9 Ó ti pín ká, ó ti fi fún àwọn olùpọ́njú,
10 Ènìyàn búburú yóò ri, inú wọn yóò sì bàjẹ́,