Oséias 4

YOR

1 Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọmọ Israẹli,

2 àfi èpè, irọ́ pípa àti ìpànìyàn

3 Nítorí èyí, ilẹ̀ náà ń ṣọ̀fọ̀,

4 “Ṣùgbọ́n kí ẹnikẹ́ni má ṣe mú ẹ̀sùn wá,

5 Ẹ ń ṣubú lọ́sàn án àti lóru

6 àwọn ènìyàn mi ń ṣègbé nítorí pé wọn kò ní ìmọ̀.

7 Bí àwọn àlùfáà ṣe ń pọ̀ sí i

8 wọ́n ń jẹun nípa ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi,

9 Yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe rí náà ni àwọn àlùfáà rí.

10 “Wọn ó máa jẹun ṣùgbọ́n wọn kò ní yó;

11 fún àgbèrè;

12 Wọ́n ń gba ìmọ̀ràn lọ́wọ́ ère igi

13 Wọ́n ń rú ẹbọ lórí àwọn òkè ńlá,

14 “Èmi kò ní jẹ àwọn ọmọbìnrin yín

15 “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o ṣe àgbèrè ìwọ Israẹli,

16 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe agídí

17 Efraimu ti darapọ̀ mọ́

18 Bí ohun mímu wọn bá tilẹ̀ tán,

19 Ìjì ni yóò gbá wọn lọ.

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado