1 Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọmọ Israẹli,
2 àfi èpè, irọ́ pípa àti ìpànìyàn
3 Nítorí èyí, ilẹ̀ náà ń ṣọ̀fọ̀,
4 “Ṣùgbọ́n kí ẹnikẹ́ni má ṣe mú ẹ̀sùn wá,
5 Ẹ ń ṣubú lọ́sàn án àti lóru
6 àwọn ènìyàn mi ń ṣègbé nítorí pé wọn kò ní ìmọ̀.
7 Bí àwọn àlùfáà ṣe ń pọ̀ sí i
8 wọ́n ń jẹun nípa ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi,
9 Yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe rí náà ni àwọn àlùfáà rí.
10 “Wọn ó máa jẹun ṣùgbọ́n wọn kò ní yó;
11 fún àgbèrè;
12 Wọ́n ń gba ìmọ̀ràn lọ́wọ́ ère igi
13 Wọ́n ń rú ẹbọ lórí àwọn òkè ńlá,
14 “Èmi kò ní jẹ àwọn ọmọbìnrin yín
15 “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o ṣe àgbèrè ìwọ Israẹli,
16 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe agídí
17 Efraimu ti darapọ̀ mọ́
18 Bí ohun mímu wọn bá tilẹ̀ tán,
19 Ìjì ni yóò gbá wọn lọ.