Jeremias 51

YOR

1 Ohùn ti Olúwa wí nìyìí:

2 Èmi yóò rán àwọn àjèjì ènìyàn sí Babeli

3 Má ṣe jẹ́ kí tafàtafà yọ ọfà rẹ̀,

4 Gbogbo wọn ni yóò ṣubú ní Babeli,

5 Nítorí pé Juda àti Israẹli ni

6 “Sá kúrò ní Babeli!

7 Ife wúrà ni Babeli ní ọwọ́ Olúwa;

8 Babeli yóò ṣubú lójijì, yóò sì fọ́.

9 “ ‘À bá ti wo Babeli sàn,

10 “ ‘Olúwa ti dá wa láre,

11 “Ṣe ọfà rẹ ní mímú,

12 Gbé àsíá sókè sí odi Babeli!

13 Ìwọ tí o gbé lẹ́bàá odò púpọ̀,

14 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti búra fún ara rẹ̀,

15 “Ó dá ilẹ̀ nípa agbára rẹ̀,

16 Nígbà tí ará omi ọ̀run hó

17 “Olúkúlùkù ènìyàn ni kò lọ́pọlọ tí kò sì ní ìmọ̀,

18 Asán ni wọ́n, àti iṣẹ́ ìsìnà,

19 Ẹni tí ó jẹ́ ìpín Jakọbu kó rí bí ìwọ̀nyí;

20 “Ìwọ ni kùmọ̀ ogun ohun èlò ogun mi,

21 Pẹ̀lú rẹ, èmi ó pa ẹṣin àti ẹni tí ó gùn ún pẹ̀lú rẹ̀;

22 pẹ̀lú rẹ, mo pa ọkùnrin àti obìnrin,

23 Èmi yóò sì fi ọ́ fọ́ olùṣọ́-àgùntàn,

24 “Ní ojú rẹ, èmi yóò san án fún Babeli àti gbogbo àwọn olùgbé inú rẹ̀ fún gbogbo ibi tí wọ́n ti ṣe ní Sioni,”

25 “Mo lòdì sí ọ, ìwọ òkè apanirun

26 A kò ní mú òkúta kankan láti

27 “Gbé àsíá sókè ní ilẹ̀ náà!

28 Sọ àwọn orílẹ̀-èdè pẹ̀lú àwọn ọba Media di mímọ́ sórí rẹ̀,

29 Ilẹ̀ wárìrì síyìn-ín sọ́hùn-ún,

30 Gbogbo àwọn jagunjagun

31 Ìránṣẹ́ kan ń tẹ̀lé òmíràn

32 Odò tí ó sàn kọjá kò sàn mọ́

33 Ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run àwọn ọmọ Israẹli sọ nìyìí:

34 “Nebukadnessari ọba Babeli tó jẹ wá run,

35 Kí gbogbo ìparun tí ó ṣe sí ẹran-ara wa wà lórí Babeli,”

36 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa wí:

37 Babeli yóò parun pátápátá,

38 Àwọn ènìyàn inú rẹ̀ bú ramúramù

39 Ṣùgbọ́n nígbà tí ọkàn wọn bá ru sókè,

40 “Èmi yóò fà wọ́n lọ gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́-àgùntàn

41 “Báwo ni Ṣeṣaki yóò ṣe dí mímú, ìfọ́nnu gbogbo àgbáyé.

42 Òkun yóò ru borí Babeli,

43 Àwọn ìlú rẹ̀ yóò di ahoro,

44 Èmi yóò fi ìyà jẹ Beli ti Babeli

45 “Ẹ jáde kúrò nínú rẹ̀

46 Má ṣe jẹ́ kí ọkàn rẹ dàrú

47 Nítorí ìgbà náà yóò wá dandan

48 Ọ̀run àti ayé àti gbogbo ohun tí ó wà nínú wọn,

49 “Babiloni gbọdọ̀ ṣubú nítorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni Israẹli,

50 Ẹ̀yin tí ó ti bọ́ lọ́wọ́ idà, ẹ lọ, ẹ má dúró.

51 “Ojú tì wá, nítorí pé àwa ti gbọ́ ẹ̀gàn:

52 “Nítorí náà, wò ó, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí,

53 Bí Babeli tilẹ̀ gòkè lọ sí ọ̀run,

54 “Ìró igbe láti Babeli,

55 Nítorí pé Olúwa ti ṣe Babeli ní ìjẹ,

56 Nítorí pé afiniṣèjẹ dé sórí rẹ̀,

57 Èmi ó sì mú kí àwọn ìjòyè rẹ̀ yó bí ọ̀mùtí,

58 Báyìí ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí:

59 Ọ̀rọ̀ tí Jeremiah wòlíì pàṣẹ fún Seraiah, ọmọ Neriah, ọmọ Maseiah, nígbà tí o ń lọ ni ti Sedekiah, ọba Juda, sí Babeli ní ọdún kẹrin ìjọba rẹ̀. Seraiah yìí sì ní ìjòyè ibùdó.

60 Jeremiah sì kọ gbogbo ọ̀rọ̀ ibi tí yóò wá sórí Babeli sínú ìwé kan, àní gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí tí a kọ sí Babeli.

61 Jeremiah sì sọ fún Seraiah pé, “Nígbà tí ìwọ bá dé Babeli, kí ìwọ kí ó sì wò, kí ìwọ kí ó sì ka gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí.

62 Kí ìwọ kí ó sì wí pé, ‘Olúwa ìwọ ti sọ̀rọ̀ sí ibí yí, láti ké e kúrò, kí ẹnikẹ́ni má ṣe gbé inú rẹ̀, àti ènìyàn àti ẹran, nítorí pé yóò di ahoro láéláé.’

63 Yóò sì ṣe, nígbà tí ìwọ bá parí kíka ìwé yìí tán kí ìwọ kí ó di òkúta mọ́ ọn, kí ó sì sọ ọ́ sí àárín odò Eufurate.

64 Kí ìwọ sì wí pé, ‘Báyìí ní Babeli yóò rì, kí yóò sì tún dìde kúrò nínú ibi tí èmi ó mú wá sórí rẹ̀: àárẹ̀ yóò sì mú wọn.’ ”

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado