1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé:
2 “Lọ kí o sì kéde sí etí Jerusalẹmu pé:
3 Israẹli jẹ́ mímọ́ sí Olúwa,
4 Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ìdílé Jakọbu
5 Báyìí ni Olúwa wí:
6 Wọn kò béèrè, ‘Níbo ni Olúwa wà,
7 Èmi mú yín wá sí ilẹ̀ ọlọ́ràá
8 Àwọn àlùfáà kò béèrè wí pé,
9 “Nítorí náà, mo fi ẹ̀sùn kàn yín lẹ́ẹ̀kan sí i,”
10 Rékọjá lọ sí erékùṣù àwọn ara Kittimu, kí ẹ sì wò ó,
11 Orílẹ̀-èdè kan ha á pa ọlọ́run rẹ̀ dà?
12 Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì
13 “Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì,
14 Israẹli ha á jẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ ẹrú nípa ìbí?
15 Àwọn kìnnìún ké ramúramù;
16 Bákan náà, àwọn ọkùnrin Memfisi àti Tafanesi
17 Ẹ̀yin kò ha a ti fa èyí sórí ara yín
18 Kí ló dé tí o ṣe wá lọ Ejibiti
19 Iṣẹ́ búburú yín yóò fìyà jẹ yín
20 “Nígbà àtijọ́, o ti fọ́ àjàgà rẹ sọnù,
21 Èmi ti gbìn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àjàrà ọ̀tọ̀,
22 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o wẹ ara rẹ pẹ̀lú sódà
23 “Báwo ni ìwọ ṣe wí pé, ‘Èmi kò ṣe aláìmọ́,
24 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tí ń gbé aginjù
25 Dá ẹsẹ̀ dúró láìwọ bàtà,
26 “Gẹ́gẹ́ bí a ṣe ń dójútì olè nígbà tí a bá mú u,
27 Wọ́n sọ fún igi pé, ‘Ìwọ ni baba mi,’
28 Níbo wá ni àwọn ọlọ́run tí ẹ ṣe fúnra yín ha a wà?
29 “Kí ló dé tí o ṣe wá ń fi ẹ̀sùn kàn mí?
30 “Nínú asán mo fìyà jẹ àwọn ènìyàn yín,
31 “Ẹ̀yin ìran yìí, ẹ kíyèsi ọ̀rọ̀ Olúwa:
32 Wúńdíá ha le gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀,
33 Ìwọ ti jẹ́ ọlọ́gbọ́n tó nípa ọ̀rọ̀ ìfẹ́!
34 Lórí aṣọ rẹ ni wọ́n bá
35 ìwọ sọ wí pé, ‘Èmi jẹ́ aláìṣẹ̀;
36 Èéṣe tí ìwọ fi ń lọ káàkiri
37 Ìwọ yóò sì fi ibẹ̀ sílẹ̀