1 Nítòótọ́, koto fàdákà ń bẹ,
2 Nínú ilẹ̀ ni à ń gbé ń wa irin,
3 Ènìyàn ni ó fi òpin si òkùnkùn,
4 Wọ́n wa ihò ilẹ̀ tí ó jì sí àwọn tí ń gbé òkè,
5 Bí ó ṣe ti ilẹ̀ ni, nínú rẹ̀ ni oúnjẹ ti ń jáde wá,
6 òkúta ibẹ̀ ni ibi òkúta safire,
7 Ipa ọ̀nà náà ni ẹyẹ kò mọ̀,
8 Àwọn ẹranko agbéraga kò rìn ibẹ̀ rí,
9 Ó fi ọwọ́ rẹ̀ lé akọ òkúta,
10 Ó sì la ipa odò ṣíṣàn nínú àpáta,
11 Ó sì ṣe ìṣàn odò kí ó má ṣe kún àkúnya,
12 Ṣùgbọ́n níbo ni á ó gbé wá ọgbọ́n rí,
13 Ènìyàn kò mọ iye rẹ̀,
14 Ọ̀gbun wí pé, “Kò sí nínú mi”;
15 A kò le è fi wúrà rà á,
16 A kò le è fi wúrà Ofiri, tàbí òkúta óníkìsì iyebíye,
17 Wúrà àti òkúta kristali kò tó ẹgbẹ́ rẹ̀;
18 A kò lè dárúkọ iyùn tàbí òkúta jasperi;
19 Òkúta topasi ti Kuṣi kò tó ẹgbẹ́ rẹ̀;
20 Níbo ha ni ọgbọ́n ti jáde wá?
21 A rí i pé, ó fi ara sinko kúrò ní ojú àwọn alààyè gbogbo,
22 Ibi ìparun àti ikú wí pé,
23 Ọlọ́run ni ó mọ òye ipa ọ̀nà rẹ̀,
24 Nítorí pé ó wòye dé òpin ayé,
25 láti dà òsùwọ̀n fún afẹ́fẹ́,
26 Nígbà tí ó pàṣẹ fún òjò,
27 nígbà náà ni ó rí i, ó sì sọ ọ́ jáde;
28 Àti fún ènìyàn ni ó wí pé,