1 Nígbà náà ni Jona gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ láti inú ẹja náà wá,
2 Ó sì wí pé:
3 Nítorí tí ìwọ ti sọ mí sínú ibú,
4 Nígbà náà ni mo wí pé,
5 Omi yí mi káàkiri, àní títí dé ọkàn;
6 Èmi sọ̀kalẹ̀ lọ sí ìsàlẹ̀ àwọn òkè ńlá;
7 “Nígbà tí ó rẹ ọkàn mi nínú mi,
8 “Àwọn tí ń fàmọ́ òrìṣà èké
9 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi orin ọpẹ́, rú ẹbọ sí ọ.
10 Olúwa sì pàṣẹ fún ẹja náà, ó sì pọ Jona sí orí ilẹ̀ gbígbẹ.