Isaías 5

YOR

1 Èmi yóò kọrin fún ẹni tí mo fẹ́ràn

2 Ó tu ilẹ̀ rẹ̀, ó ṣa òkúta ibẹ̀ kúrò

3 “Ní ìsinsin yìí ẹ̀yin olùgbé Jerusalẹmu

4 Kín ni ó kù tí n ò bá túnṣe sí ọgbà àjàrà mi.

5 Ní ìsinsin yìí, èmi yóò wí fún ọ

6 Èmi yóò sì sọ ọ́ di ahoro

7 Ọgbà àjàrà Olúwa àwọn ọmọ-ogun

8 Ègbé ni fún àwọn tí ń kọ́lé mọ́lé

9 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti sọ ọ́ sí mi létí:

10 Ọgbà àjàrà sáré oko mẹ́wàá yóò mú

11 Ègbé ni fún àwọn tí wọ́n dìde

12 Wọ́n ní dùùrù àti ohun èlò orin olókùn níbi àsè wọn,

13 Nítorí náà àwọn ènìyàn mi yóò lọ sí ìgbèkùn

14 Nítorí náà isà òkú ti ń dátọ́mì gidigidi,

15 Báyìí, ènìyàn yóò di ìrẹ̀sílẹ̀

16 Ṣùgbọ́n Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni a ó gbéga nípa ẹ̀tọ́ rẹ̀,

17 Nígbà náà ni àwọn àgùntàn yóò máa jẹ́ ko ní ibùgbé e wọn,

18 Ègbé ni fún àwọn tí ń fi ohun asán fa ẹ̀ṣẹ̀,

19 sí àwọn tí ó sọ pé, “Jẹ́ kí Ọlọ́run ṣe kíákíá,

20 Ègbé ni fún àwọn tí ń pe ibi ní rere, àti rere ní ibi,

21 Ègbé ni fún àwọn tí ó gbọ́n lójú ara wọn

22 Ègbé ni fún àwọn akọni nínú wáìnì mímu

23 tí wọ́n dá ẹlẹ́bi sílẹ̀ nítorí àbẹ̀tẹ́lẹ̀,

24 Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí ahọ́n iná ṣe ń jó àgékù koríko run

25 Nítorí náà, ìbínú Olúwa gbóná si àwọn ènìyàn rẹ̀,

26 Yóò sì gbé ọ̀págun sókè sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ó jìnnà,

27 Kò sí ẹni tí yóò rẹ̀ nínú wọn, tàbí tí yóò kọsẹ̀,

28 Àwọn ọfà wọn múná,

29 Bíbú wọn dàbí tí kìnnìún,

30 Ní ọjọ́ náà, wọn yóò hó lé e lórí

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado