1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
2 “Ọmọ ènìyàn, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí sí ilé Israẹli:
3 Òpin tí dé sí ọ báyìí,
4 Ojú mi kò ní i dá ọ sì,
5 “Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí:
6 Òpin ti dé!
7 Ìparun ti dé sórí rẹ,
8 Mo ṣetán láti tú ìbínú gbígbóná mi lé ọ lórí
9 Ojú mi kò ní i dá ọ sí,
10 “ ‘Ọjọ́ náà dé!
11 Ìwà ipá ti di ọ̀pá ìwà búburú;
12 Àkókò náà dé!
13 Nítorí pé òǹtajà kì yóò rí gbà padà
14 “ ‘Wọ́n ti fọn ìpè ogun,
15 Idà wà ní ìta,
16 Gbogbo àwọn tí ó bọ́ nínú wọn yóò sálà,
17 Gbogbo ọwọ́ yóò rọ,
18 Wọn yóò wọ aṣọ ọ̀fọ̀,
19 “ ‘Wọn yóò dà fàdákà wọn sí ojú pópó,
20 Wọ́n ń ṣe ìgbéraga pẹ̀lú ohun ọ̀ṣọ́ wọn tí ó lẹ́wà,
21 Èmi yóò sì fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣe ìjẹ fún àjèjì
22 Èmi yóò gbójú mi kúrò lára wọn,
23 “ ‘Rọ ẹ̀wọ̀n irin!
24 Èmi yóò mú kí orílẹ̀-èdè ti ó búburú jùlọ
25 Nígbà tí ìpayà bá dé,
26 Wàhálà lórí wàhálà yóò dé,
27 Ọba yóò ṣọ̀fọ̀,