Ezequiel 19

YOR

1 “Kọ orin ọ̀fọ̀ nítorí àwọn ọmọ-aládé Israẹli

2 wí pé:

3 Ó sì tọ́ ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ dàgbà, ó sì di kìnnìún tó ní agbára,

4 Àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ nípa rẹ̀,

5 “ ‘Nígbà tí abo kìnnìún yìí rí pé ìrètí rẹ̀ sì jásí asán,

6 Ó sì ń rìn káàkiri láàrín àwọn kìnnìún nítorí pé ó ti lágbára,

7 Ó sì wó odi wọn palẹ̀ ó sì sọ àwọn ìlú wọn di ahoro.

8 Nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè dìde sí i,

9 Wọn fi ìwọ̀ gbé e sínú àgò, wọn mú un lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babeli,

10 “ ‘Ìyá rẹ dàbí àjàrà nínú ọgbà àjàrà rẹ̀;

11 Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ lágbára tó láti fi ṣe ọ̀pá àṣẹ ìjòyè,

12 Ṣùgbọ́n ó fà á tu ní ìrunú,

13 Báyìí, a tún ún gbìn sínú aṣálẹ̀

14 Iná sì jáde láti ọ̀kan lára ẹ̀ka rẹ̀

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado