1 “Kọ orin ọ̀fọ̀ nítorí àwọn ọmọ-aládé Israẹli
2 wí pé:
3 Ó sì tọ́ ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ dàgbà, ó sì di kìnnìún tó ní agbára,
4 Àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ nípa rẹ̀,
5 “ ‘Nígbà tí abo kìnnìún yìí rí pé ìrètí rẹ̀ sì jásí asán,
6 Ó sì ń rìn káàkiri láàrín àwọn kìnnìún nítorí pé ó ti lágbára,
7 Ó sì wó odi wọn palẹ̀ ó sì sọ àwọn ìlú wọn di ahoro.
8 Nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè dìde sí i,
9 Wọn fi ìwọ̀ gbé e sínú àgò, wọn mú un lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babeli,
10 “ ‘Ìyá rẹ dàbí àjàrà nínú ọgbà àjàrà rẹ̀;
11 Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ lágbára tó láti fi ṣe ọ̀pá àṣẹ ìjòyè,
12 Ṣùgbọ́n ó fà á tu ní ìrunú,
13 Báyìí, a tún ún gbìn sínú aṣálẹ̀
14 Iná sì jáde láti ọ̀kan lára ẹ̀ka rẹ̀