1 Orúkọ rere sàn ju ìpara olóòórùn dídùn lọ,
2 Ó dára láti lọ sí ilé ọ̀fọ̀
3 Ìbànújẹ́ dára ju ẹ̀rín lọ,
4 Ọkàn ọlọ́gbọ́n wà ní ilé ọ̀fọ̀,
5 Ó dára láti gba ìbáwí ọlọ́gbọ́n,
6 Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀gún ti ń dún lábẹ́ ìkòkò
7 Ìrẹ́jẹ a máa sọ ọlọ́gbọ́n di òmùgọ̀,
8 Òpin ọ̀rọ̀ dára ju ìbẹ̀rẹ̀ rẹ̀ lọ,
9 Má ṣe yára bínú ní ọkàn rẹ
10 Má ṣe sọ wí pé, “Kí ni ìdí tí àtijọ́ fi dára ju èyí?”
11 Ọgbọ́n, gẹ́gẹ́ bí ogún ìní jẹ́ ohun tí ó dára
12 Ọgbọ́n jẹ́ ààbò
13 Wo ohun tí Ọlọ́run ti ṣe:
14 Nígbà tí àkókò bá dára, jẹ́ kí inú rẹ dùn,
15 Nínú ayé àìní ìtumọ̀ yìí ni mo ti rí gbogbo èyí
16 Má ṣe jẹ́ olódodo jùlọ
17 Ìwọ ma ṣe búburú jùlọ kí ìwọ má sì ṣe aṣiwèrè,
18 Ó dára láti mú ọ̀kan
19 Ọgbọ́n máa ń mú kí ọlọ́gbọ́n ènìyàn ní agbára
20 Kò sí olódodo ènìyàn kan láyé
21 Má ṣe kíyèsi gbogbo ọ̀rọ̀ tí ènìyàn ń sọ
22 Tí o sì mọ̀ nínú ọkàn rẹ
23 Gbogbo èyí ni mo ti dánwò nípa ọgbọ́n, tí mo sì wí pé,
24 Ohun tí ó wù kí ọgbọ́n le è jẹ́,
25 Mo wá rò ó nínú ọkàn mi láti mọ̀,
26 Mo rí ohun tí ó korò ju ikú lọ
27 Oniwaasu wí pé, “Wò ó, eléyìí ni ohun tí mo ti ṣàwárí:
28 Nígbà tí mo sì ń wá a kiri
29 Eléyìí nìkan ni mo tí ì rí: